Thursday, July 6, 2023
Home
Unlabelled
YORUBA COUNCIL OF YOUTH WORLDWIDE (YCYW) KI BABA RERE, DISTINGUISHED HON IBRAHIM AYOKUNLE ISIAKA (MHR IFO/EWEKORO ), AARE ASOJU OODUA LAGBAYE, ASOLUDERO OF EGBALAND,KU ORIIRE ỌJỌ IBI
YORUBA COUNCIL OF YOUTH WORLDWIDE (YCYW) KI BABA RERE, DISTINGUISHED HON IBRAHIM AYOKUNLE ISIAKA (MHR IFO/EWEKORO ), AARE ASOJU OODUA LAGBAYE, ASOLUDERO OF EGBALAND,KU ORIIRE ỌJỌ IBI
Ni Orúkọ Gbogbo Igbimọ Ọdọ Yorùbá Lágbayé ẹka tí Ipinlẹ Ogun labẹ Àṣẹ Alaga wa AsojuOdo Omoluabi Sunday Adebowale a ki baba wa, baba rere, Distinguished Hon IBRAHIM ISIAKA, (MHR Ifo/Ewekoro Federal constituency) ku ayẹyẹ ọjọ ìbí wọn loni ọjọ kefa (6), Oṣu keje (July), ọdún 2023
A si gba ni adura npe ki ọlọrun tún bọ máa b'awa lọra ẹmi yin ninu ọlá, ninu ipo, ninu ọgbọn àti oye ti ẹ fi tunbọ máa ṣe ìlú ifo/Ewekoro lọ síwájú si, paapa julọ ninu àìkú baálẹ̀ ọrọ.
Lẹẹkansi ẹku oriire ọjọ ibi, ẹmi yin aṣe púpọ ọdún láyé, lágbára ọlọrun àti àwọn tó tẹ ilẹ yorùbá dó. Àṣẹ!
A si tun fi akoko yi dupẹ lọwọ yin Lẹẹkansi fún ipa ribiribi ti ẹtì nko l'agbo òṣèlú ati ìdàgbàsókè ,ifo/Ewekoro, ipinlẹ Ogun, paapa julọ ni ẹka ti idagbasoke ati ofin sise Nile igbimo asofu agba l'abuja fun gbogbo orilẹ-ède Naijiria lapapọ, ẹ ṣe gan adupẹ, ki ọlọrun bawa kun yin lọwọ.
Ọmọ Yorùbá ni mí, Ọmọ kaarọ ojiire!
Fún igbimọ ọdọ ipinlẹ ogun,
E-signed:
AsojuOdo Omoluabi Sunday Adebowale
Chairman, YCYW Ogun State Council
Through:
Omoluabi Yusuf Wasiu Olamilekan
(Oko Momi)
Media and Publicity Secretary, YCYW, Ogun State
Ycywogunstate@gmail.com
6/7/2023
About NeighborhoodMic
Author Details
Tiwalade Gbenga Gabriel is a graduate of Industrial Chemistry, holds a Diploma in Business Administration, and is a Fellow of the Institute of Customer Relations Management.
He currently serves as the Special Assistant to the Chairman of Ikenne Local Government on New Media, where he contributes to strategic digital communication, media engagement, and the effective dissemination of information across various platforms.